It is no longer news that the Governor of Lagos State, Akinwunmi Ambode, has ordered that schools - Private and Public - in the state must sing the Yoruba version of the National Anthem daily on the assembly, as part of efforts to deepen the cultural identity of the land.
Here is the approved version
VERSE 1
Dide eyin ara
Waka je ipe Naijiria
K'a fife sin 'le wa
Pel'okun at'sigbagbo
Kise awon akoni wa,
ko mase ja s'asan
K'a sin t'okan tara
Ile t'ominira,at'al
aafia
So d'okan
VERSE 2
Olorun Eleda
To ipa ona wa
F'ona han asaaju
K'odo wa m'otito
K'ododo at'ife po sii
K'aye won je pipe
So won d'eni giga
K'alafia oun eto le
Joba ni 'le wa
THE PLEDGE
Mo se ileri fun Orile-Ede mi Naijiria,
Lati je olododo, eniti o see f'okan tan
Ati olotito eniyan
Lati sin in pelu gbogbo agbara mi,
Lati sa ipa mi gbogbo fun isokan re
Ati lati gbe e ga fun iyi ati ogo re.
Ki Olorun ran mi l'owo
Here is the approved version
VERSE 1
Dide eyin ara
Waka je ipe Naijiria
K'a fife sin 'le wa
Pel'okun at'sigbagbo
Kise awon akoni wa,
ko mase ja s'asan
K'a sin t'okan tara
Ile t'ominira,at'al
aafia
So d'okan
VERSE 2
Olorun Eleda
To ipa ona wa
F'ona han asaaju
K'odo wa m'otito
K'ododo at'ife po sii
K'aye won je pipe
So won d'eni giga
K'alafia oun eto le
Joba ni 'le wa
THE PLEDGE
Mo se ileri fun Orile-Ede mi Naijiria,
Lati je olododo, eniti o see f'okan tan
Ati olotito eniyan
Lati sin in pelu gbogbo agbara mi,
Lati sa ipa mi gbogbo fun isokan re
Ati lati gbe e ga fun iyi ati ogo re.
Ki Olorun ran mi l'owo
Comments
Post a Comment